Saturday, December 31, 2022

Ẹ kaabọ̀ si ìlú Slvador, Ojogbọ́n Babalawo Ogundeji Ifadamitan Elebuibon!



Mo ki eyin baba mi, mo ki eyin Ìyá mi.

Mo ki eyin Ẹgbọn mi ati aburo mi fún ayeye ọdún yìí.

Mo bÈù lẹ́gbára,ki ó fún wa ni ọ̀na ti o dará, ti o si ye kooro.

Jẹ́ ki a ki Èṣù ni ṣaaju ki a sọ̀rọ̀ nipa ohunkohun ninu èto wa loni:

 

Ago,



Mo júbà Èṣù

Èṣù, Mo júbà

Ẹlẹ́gbára ri ajagbọn wa ti o farasin

 Araketu náà ti o ń sọ̀rọ̀ ń sọ̀rọ̀

Èṣù jinnijinni

Kò gba

Laroye!

 

Mo dúpẹ́ Oluwo Awoosore Ifdamitan Daniel Diniz ti wọn ń pe mi lati kopa ninu ipade yìí.

 

Emi ni ọmọ Oduduwa.

Mo ki yin ọmọ ìyá mi kaakiri àwọn orílẹ̀èdè lagbaye

Ẹ ku ọdún tuntun!  

Orúkọ̀ mi ni Adelson Adewale de Brito ti ọpọlọpọ ènìyàn mọ̀ si Ọ̀mọ̀wé Adelson tabi Mọ̀wé Adelson tabi Mawo Adelson.

Mo ki gbogbo ilé, Ẹ kaasan!

Mo ki dọ́kità Ogundeji Ifadamitan Elebuibon

Ẹ kaabọ̀ Ojogbọ́n!

Mo ki yin Ẹ káàbọ̀ pẹ̀lu inudidun pe Mo lo èdè àwọn Bàbá nlá wa lati ki yin “Ẹ́ káàbọ̀” si ìlú Salvador, Olu-ìlú ipinlẹ̀ Baííà.

Ìlú Salvador jẹ́ ìlú ti àwọn aláwọ̀ dúdú pọ̀ jùlọ lagbaye lẹ́hìn Afrika.

Ẹ ku joko, Ojobọn!

Ọmọ orílẹ̀ede Brasili ni mi, ṣùgbọ́n, Mo yangan pe iran Ànàgó ni mi. Emi jẹ́ ara ipelẹ̀ akoko ninu  iran Ànàgó ti wọn mu wa si orílẹ̀ede yìí laarin ni ọgọ́run mẹ́ta ọdún sẹ́hìn, lasiko òwò ẹrú. Olúkọ̀ èdè ati àṣà Ànàgó ni mi.

Ojogbọ́n Ogundeji, Mo ki yin Ẹ kaabọ̀ lorúkọ temi ati lorúkọ àwọn ọmọ ìlú yìí paapa jùlọ̀ lorúkọ̀ àwọn aláwọ̀ dúdú.

Mo tọrọ gafaara lati dúpẹ́ gidigidi iṣẹ lati ọwọ́ olori ẹsin Ifa náà Babalawo Awosoore Ifadamitan Daniel Diniz “Ẹ ku iṣẹ takun takun, Oluwo”. Mo bẹ́ Ogbọ́n Ọ̀rùnmílá búkun sorí ẹ loni ati lọla ati gbogbo ọjọ́ laarin igbesiaye ẹ.

A kò gbọ̀dọ́ gbàgbé wipe ọdún yìí lọ sọpin. Ọla ni Ọjọ́ tó Ṣáájú Ọdún Tuntun. Bẹ́ẹ̀ni, Ọjọ́ Aiku to nbọ jẹ́ ọjọ́ kinni, oṣu kinni ọdún tuntun.

So, Ọjọ́ Aiku ni ọjọ́ isinmi akọkọ ni eyi ti onikaluku fi sami ayajọ pe oju koowa ri ọdún tuntun.

Mo gbadúrà wipe ọwọ́ ọlọ́rún itura yoo kọ fún olukaluku wa irọrún , aseyori ati alaafia ni gbogbo ìgbà laarin ọdún to ń bọ́.

A kò gbọ̀dọ́ gbàgbé dúpẹ́ fún ni ọwọ́ Ẹlẹ́da wa fún aye wa.

Ojogbọ́n Ogundeji, Emi ò mọ̀ boya yin mọ pe ipinlẹ̀ Baííà jẹ́ Olú-ìlú Yorùbá fún gbogbo àwọn Amẹ́rika...

Ni ọjọ́ kewa, oṣù kẹfà, ọdún 2018 lára abẹwo si orílẹ̀-èdè Brasíìlì, Ọọni ile-Ifẹ náà, Ọba Adeyẹye Ogunwusi Ọjaja keji wa si ìlú Salvador lati fi ipinlẹ̀ Baííà lelẹ̀ gẹgẹ̀ bi Olú-ìlú Yorùbá fún gbogbo àwọn Amẹ́rika.

Lati isisiyi lọ Emi yoo sọ ni èdè Oyinbo ati Pọtọgi fún anfaani àwọn ti ko gbọ Yorùbá.

Ẹ ṣẹun Mo dúpẹ!




Wednesday, November 16, 2022

The Ànàgó is spoken in Salvador Bahia, the Yoruba Capital of the Americas

 


The Ọọ̀ni Ilè-Ifẹ̀, His Imperial Majesty, Dr. Adeyeye Babatunde Enitan Ogunwusi, the Ojaja II,arrived at Luís Eduardo Magalhães International Airport in Salvador city, the Capital of Bahia state, on June 8, 2018, The word Ọọ̀ni is a reference to the contraction of words in the phrase “Ọ ní òrìṣà” which means “He is in Orisha” or “He speaks Orisha” or “He is Orisha”.

It is up to the Ọọ̀ni Ilè-Ifẹ̀ to primarily care for the four hundred plus one (400+1) Orisha, as High Priest of the World Cult of Orisha and traditional Ruler of Ile-Ifè, a city-state in Nigeria that is recognized as the craddle of the Yoruba people and civilization.

Some Candomblé temples in our city have direct ancestral links with the  kingdom of Ilè-Ifẹ̀ and it was in this sense that He visited the Ilê Odo Ogé Temple better known as Pilão de Prata, whose religious leader is Babalorixá Air José Sowzer, a direct descendant of Bamboshe an important African babalawo in the history of the African diaspora. Babalorishá Air José Sowzer appears in the image that illustrate that article, on the extreme right of the photo, while the author of this post appears on the extreme left.

This image was captured by the lens of the photographer of Jornal Correio da Bahia (Bahia Mail Newspaper) on June 10, at the emblematic Igreja da Barroquinha, in our Salvador, Capital of the State of Bahia, when Ooni Adeyeye declared Bahia as: “Bahia, Yoruba Capital of Americas”. Also appearing in the photo, in addition to those already mentioned, from left to right, Dr. Arani Santana, State Secretary of Culture, Dr. Francisco de Assis, representing the Gregório de Matos Foundation (Secretary of Culture on the city level), the Ooni of Ilé-Ifé, His Majesty Adeyeye Babatunde Ogunwusi, and Dr Fábya Reis, State Secretary for the Promotion of Racial Equality.

One of the main objectives of the visit was to strengthen the existing cultural affinities between Afro-descendants in Brazil and Yoruba and Yoruba Afrodescendents people in Nigeria, with a view to using the common cultural heritage in favor of a cultural and economic partnership that will benefit both countries.

At the official reception on the same occasion, we had the opportunity to address the Ooni by saluting with speaking the language of our grand parentes in Ànàgó, saying:

Ẹ káààsan

Orukọ temi Ni Professor Adelson de Brito ti ọpọlọpọ ènìyàn mọ si Mawo Adelson. Mo Ki Kabiyesi ọba Adeyeye Enitan Babatunde Ogunwusi Ojaja II, ni orúkọ temi ati lorukọ gbogbo ẹgbẹ Ilê Odo Ogé

Mo ki gbogbo awọn ọmọkunrin ati awọn awọn ọmọbiri

Kábiyèsí o, ọba aláṣẹ, ikeji òrìṣà, ki adé pẹ lórí, ki bàtà pẹ lẹsẹ, ki ìrùkẹrẹ pẹ lọwọ,

Ki ẹṣin ọba jẹ ko pẹ o, Kábiyèsí o"

Odùdúwà gbe wa o, Baba

Kábiyèsí oooo!

Ẹ kàábọ̀!

 

Translation

 

Good afternoon.

Greetings to all ladies and gentlemen.

Hail, His Majesty, mighty King (owner of the asé), second person of the gods, Hail the Crown that adorns Your noble head, Hail the Footwear under Your feet. Hail the Irukere that you hold in your hand. May your horse have the strength to carry you / may you have long life. Hail, Oh, Majesty,

My name is Professor Adelson better known as Mawo Adelson.

I salute His Majesty King Ooni Adeyeye Enitan Babatunde Ogunwusi Ojaja II,

Welcome!